Nítorí ọ̀wọ́ngógó epo bẹntiróòlù Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ẹ́ kó ọkọ̀ tó n lo afẹ́fẹ́ gáàsì síta

  • 📰 TheNationNews
  • ⏱ Reading Time:
  • 46 sec. here
  • 2 min. at publisher
  • 📊 Quality Score:
  • News: 22%
  • Publisher: 69%

Nigeria Headlines News

Nigeria Latest News,Nigeria Headlines

The Nation Newspaper Nítorí ọ̀wọ́ngógó epo bẹntiróòlù Ìjọba àpapọ̀ fẹ́ẹ́ kó ọkọ̀ tó n lo afẹ́fẹ́ gáàsì síta

Awọn agba bọ wọn ni ailaṣọ lọrun Paaka, o to apero gbogbo ọmọ erinwo. Owe yii lo ṣe rẹgi pẹlu igbesẹ kan ti ijọba apapọ ilẹ wa n gbe pẹlu bi wọn ṣe ni pe amulo ọkọ to n lo afẹfẹ gaasi yoo mu adinku ba ọwọngogo ounjẹ to n ṣẹlẹ lorileede yii lọwọlọwọ.

Ṣe lọjọ Abamẹta, Satide, ọsẹ to kọja ni igbakeji aarẹ, Kashim Shetima, ṣalaye pe atunṣe ti ijọba apapọ ṣe sọrọ owo ori ki i ṣe lati fi ara ni wọn, bi ko ṣe igbesẹ kan ti yoo ṣe gbogbo ọmọ orileede yii lanfaani ni.O jọ pe ọrọ yii ni Ẹdun gunle nitori alaye ti oluranlọwọ pataki si Aarẹ Bọla Ahmed Tinubu, Temitọpẹ Ajayi, ṣalaye pe ṣe ni minisita ọhun ṣelerii pe laipẹ yii ni awọn ọmọ ilẹ Naijiria yoo jẹ anfaani awọn ọkọ to n lo afẹfẹ gaasi yii.

Ṣe l’Ọjọbọ, Tọsidee, ọsẹ to kọja, ni ẹni to jẹ aarẹ ẹgbẹ awọn oṣiṣẹ lorileede yii , iyẹn Joe Ajaero, ṣabẹwo sileeṣẹ iroyin ‘The Nation’. Asiko abẹwo ọhun ni aarẹ ẹgbẹ oṣiṣẹ yii ni pe ọwọngogo owo ọkọ ko ba ma ṣẹlẹ lorileede yii rara ka ni ijọba apapọ ti ko awọn ọkọ to n lo afẹfẹ gaasi sita lọpọ yanturu. O ni “nigba ti ijọba yii de ti wọn si yọ owo iranwọ ori epo bẹntiroolu, ẹgbẹ oṣiṣẹ dabaa amulo ọkọ CNG, iyẹn awọn ọkọ to n lo afẹfẹ gaasi fun wọn.

 

Thank you for your comment. Your comment will be published after being reviewed.
Please try again later.
We have summarized this news so that you can read it quickly. If you are interested in the news, you can read the full text here. Read more:

 /  🏆 6. in NG

Nigeria Latest News, Nigeria Headlines

Similar News:You can also read news stories similar to this one that we have collected from other news sources.

Ìjọba àpapọ̀ gbọ́dọ̀ ṣàfikún owó orí tí wọ́n fi n kún ọjàThe Nation Newspaper Ìjọba àpapọ̀ gbọ́dọ̀ ṣàfikún owó orí tí wọ́n fi n kún ọjà - Oyedele
Source: TheNationNews - 🏆 6. / 69 Read more »

Oko poly reacts to alleged exam fee hike, students’ protestThe management of Federal Polytechnic, Oko, Anambra State, has reacted to a recent protest by students of the institution over allegation of a hike in examination fee. The students, in a protest last week, had accused the management of imposing a N5,000 examination fee on them.
Source: DailyPostNGR - 🏆 11. / 59 Read more »

Rivers crisis: New Speaker Victor Oko pledges loyalty to FubaraThe new Speaker of the Rivers State House of Assembly, Victor Oko, has expressed his loyalty to Governor Sim Fubara. Oko said the new state assembly under him would work with him and the people of the state.
Source: DailyPostNGR - 🏆 11. / 59 Read more »

Fresh Crisis Rocks Rivers Assembly, Pro-Fubara Lawmakers Elect Oko-Jumbo SpeakerThe Latest News from Nigeria and Around the World
Source: channelstv - 🏆 7. / 63 Read more »

Rivers Crisis: Two members of House of Assembly elect new SpeakerLawmakers loyal to Governor Siminalayi Fubara on Wednesday elected Hon. Victor Oko Jumbo as the Speaker of the Rivers State House of Assembly.
Source: DailyPostNGR - 🏆 11. / 59 Read more »

Rivers Assembly members loyal to Fubara elects new speakerThe member representing Bonny State Constituency, Victor Oko-Jumbo, has emerged as the new Speaker of the 10th Rivers State House of Assembly.
Source: GuardianNigeria - 🏆 1. / 94 Read more »